SlideShare a Scribd company logo
1 of 2
Download to read offline
“A kò gbọdọ lo ẹsìnláti fa
ìyapa, láti fi ìyà jẹni, tàbiláti
lo àǹfàní tí kò tọ”
4th
January, 2015
“Orílẹ-èdè Nàìjíríà tí a ni lọkàn jẹ èyí tí
gbogbowa á le jọjòkó ƴọayọ ìdùnnú, kí
á dì jọdúpẹ lọwọ Olọrunpapọ. Bí ó ti yẹ
kí ó rí nìyẹn”
4th
January, 2015
“Ojúṣe ìjọba ni láti pèsè ààbò àti
ìfọkàn balẹ fún gbogboọmọ Nàìjíríà
láìfi ti ẹsìn, ẹyà àti èdè ṣe. Ohùn tí a
gbọdọ pawọpọ ṣe ni, ní pàtàkì jùlọ ní
ọjọ òní tí à ń ṣe ìdúpẹ”
4th
January, 2015
“Ìgbàgbọ mi láti ìbèrè ayé mí ni wípé
gbogbo ọmọ orílẹ-èdè Nàìjíríà
gbọgbọ ní òmìnira ẹsìn láti sin Ọlọrun
gẹgẹ bí ìgbàgbọ wọn”
4th
January, 2015
“Ojúṣe ìjọba kìí ṣe ti ẹsìn”
4th
January, 2015.
Buhari
Nípa Èsìn
www.actnow.ng
“Inú mi dùn láti ríi wí pé ìsìn ìdúpẹ
ọlọdọọdún yìí, bí ó tilẹ jẹ pé ìsìn ẹsìn
Kírísítéẹnì ni, síbẹ o kó gbogbo ẹlẹsìn
papọ. Kírísítẹnì, Mùsùlùmí àti gbogbo
ẹsìn tí ó kù ni wọn ń darapọ níbí lọdọọdún
láti dúpẹ lọwọ Ọlọrun. Bí ó ṣe yẹ kí ó rí nìyí”
4th January, 2015.
Kín Ni Èrò Bùhárí Nípa Ѐsìn?
“Àwòrán fọnrán tí wọn fi sórí ẹrọ
agbọrọkáyé fi wọn hàn gẹgẹ bíi elérò
kúkúrú. Ó fi irú ènìyàn tí wọn jẹ hàn; irú
wọn kò le ṣẹrù bàwá tàbí dúnkokò mọ
òmìnira wa . Ọrọ ẹnu wọn ti fi hàn
gbangba wí pé wọn kìí ṣe ènìyàn Ọlọrun.
Wọn kò ní èrò rere fún ọrílẹ-èdè wa àti
àwa ènìyàn ibẹ. Mùsùlùmí ni mi. Mo ní
ìmọ ẹsìn kírísítẹnì mo sì mọ wí pé ẹsìn
méjéèjì ń wá àgbéjọpọ àlàáfíà fún ọmọ
ènìyàn”
Vanguard; 8th May, 2014.
Ǹjẹ Alákatakítí Ẹsìn Mùsùlùmí Tí Ó Fẹ Sọ
Orílẹ-èdè Nàìjíríà Di Ẹlẹsìn Mùsùlùmí ni
Buhari?
Ní nǹkan bíi ọdún márùn-ún sẹyìn ni wọn bẹrẹ sí ní fi
ẹsùn kan Ọgágun Muhammadu Buhari wí pé alákatakítí
ẹsìn Mùsùlùmí ni àti wí pé ó fẹ sọorílẹ-èdè yìí di ti ẹlẹsìn
Mùsùlùmí. Ẹ jẹ kí á wo àwọn òtítọ tí ó fi ojú hàn:
Òtítọ Ibẹ
• Bùhárí kò fi ìgbà kan sọ wí pé òun á mú ìṣèjọba nira
fún ìjọba ilẹ Nàìjíríà.
• Ọkan nínú àwọn Olóyè Ẹgbẹ PDP Alhaji Lawal Kaita
ló sọ wí pé ìsàkóṣo ìjọba ilẹ Nàìjíríà á nira látiṣe lẹyìn
ìdìbò ọdún 2011.
• Irọ ni Rueben Àbàtì tí ó jẹ amúgbálẹgbẹẹ Ààrẹ lórí
ètò Ìròyìn pa wí pé Bùhárí ló sọbẹẹ.
Kín Ni Bùhárí Ṣe Nípa Irọ Àbàtì Yìí?
• Bùhárí pe Àbàtì àti ìwé Ìròyìn Guardian (tí ó
tẹìròyìnnáà jáde) ní ẹjọ ìbanilórukọjẹ sí ilé ẹjọ gíga
(ṅumber ẹjọ yẹn ni ID837/2011).
• Bùhárí gbà láti gbé ẹjọ kúrò nílé ẹjọ nítorí pé
Jonathan bẹ Bùhárí.
• Ní ọjọ Kọkànlá Oṣù Keje ọdún 2013 (11-7-2013) ìwe]
ìròyìn Guardian tẹ àtẹjáde níbití Àbàtì tigbà wí pé
irọ niòun pa mọ Bùhárí, ó sì tọrọ àforíjì.
Ǹjẹ Bùhárí kórìíra àwọn ẹlẹsìn mìíràn?
• Nígbà tí ó jẹ olórí orílẹ-èdè yìí, mọkànlá (11) nínú
àwọn Gómìnà mọkàndínlógún (19) tí ó yàn sí ipò
Gómìnà, ẹlẹsìn Kírísítẹẹnì niwọn. Púpọ nínú àwọn tọ
ń bá Bùhárí siṣẹ àti àwọn òsìṣẹ inú ilé rẹ, kírísítẹẹnì
niwọn.
• Bùhárí nígbàgbọ wí pé kò yẹkí orílẹ-èdè Nàìjíríà fi
aramọ ẹsìn kan ṣoṣo, dípò bẹẹ, kí á fi ààyè gba
olúkálukú láti ṣe ẹsìntí ó bá fẹ. Torí ìdí èyí ló ṣe kọ
láti jẹ kí Orílẹ-èdè Nàìjíríà darapọ mọ ẹgbẹ
Orílẹ-èdè Ẹsìn Mùsùlùmí Agbaiyé (OIC).
Bùhárí kò kórìíra àwọn tí kìí ṣe
ẹlẹsìn Mùsùlùmí!
Olórí tí ó fi ọkàn sin ọrílẹ-èdè Nàìjíríà ni. Ó kó ènìyàn
mọra, ó sì tisiṣẹ pọ pẹlú ọpọlọpọ ọmọ Nàìjíríà láìfi ti
ẹsìn tàbí ẹyà ṣe. Àwọn olórí méjì tí ó súnmọ Bùhárí
dáadáa ni Ọgágun Yàkúbù Gowon àti Theophilus
Danjuma GCON. Ẹlẹsìn Kírísítẹnì ni àwọn méjéèji, wọn
sì wà láyé, ẹnití ó bá fẹ mọ òtítọ bóyá alákatakítí ẹsìn
Mùsùlùmí n iBùhárí tàbí bẹẹ kọ, kí ó lọbí wọn.
Kín Ni Bùhárí Sọ Nípa Boko Haram?
“Ìwà ìkà nikí á máa fi àdó olóró pa ènìyàn ní
gbogbo ìgbà. Ó burú jáì láti huirú ìwà yìí lọjọ
ọdún Kérésì, gbogbo ẹni tó bá nífẹẹ àlàáfíà ló
yẹkí ó bu ẹnuàtẹ lu iwà ìkà yìí, kí wọnsì bèèrè
fún wíwá àwọn ọdaràn wọnyí kànláti fi wọn
jófin” Ìwé Ìròyìn
This Day Life; 26th December, 2012.
“N kò mọ ọmọ ẹgbẹ Boko Haram
Kankan. N kò gbàgbọ nínú ìpànìyàn,
n kò sì mọ ẹsìn Kankan tí á lọ pa
ènìyàn, sun ilé-ẹkọníná”
Punch 8th November, 2012
Kínṅi Ó Yẹ Kí O jẹ Ojúṣe
Àwọn Olórí Ẹsìn?
SỌ ÒTÍTỌ!!!
“ahọn gbogbo àwọn wòlíì orílẹ-èdè yìí gbọdọ tú,
gbogbo àwọn ẹnu tí a ti padé gbọdọ là, bí wọn bá ti
pa ọ lẹnumọ, pọ ohun tí wọn fi dí ọ lẹnu kí o sọrọ
nítorí ọjọ iwájú àwọn ọmọ wa - - Bí jíjẹ olórí bàbá mi
bá máa mú ìparun bá àwọmọmọ, jẹ kí àjòjì kúkú ṣe
olórí kí ìran wasì wà”
“Bí baba bá ń jẹ àjẹyó, tí ebi sì ń pa àwọn ọmọ,
ǹjẹ irú ẹni bẹẹ yẹní gégé baba bi?”
RevF.R. Ejike Mbaka 31st December, 2014
“Àwọn Olùsọ Àgùtànkan ń jẹ àṣáró Jákọbù,
wọn sì ń ta àsọtẹlẹ wòlíì: wọn ń fi ìfàmìòróró
yàn se òwò ní Aso Rock --- àwọnkanń gbé
owó ilẹ wa, wọn ń sọ ọ di owó Dọlà nínú
ọkọ òfurufú aládàáni, wọn ń gbé e jáde
lọkùrò lórílẹ-èdè”
Rev F.R. EjikeMbaka 31st December, 2014

More Related Content

Viewers also liked

Viewers also liked (8)

τουρκοι βυαντινοι
τουρκοι   βυαντινοιτουρκοι   βυαντινοι
τουρκοι βυαντινοι
 
Accion tu 1_
Accion tu 1_Accion tu 1_
Accion tu 1_
 
çAğrı karaörs ab
çAğrı karaörs abçAğrı karaörs ab
çAğrı karaörs ab
 
Lenguaa1
Lenguaa1Lenguaa1
Lenguaa1
 
Best of HOUZZ 2015_Design
Best of HOUZZ 2015_DesignBest of HOUZZ 2015_Design
Best of HOUZZ 2015_Design
 
PROFRESSOR YEMI OSINBAJO LETTER TO YOU
PROFRESSOR YEMI OSINBAJO LETTER TO YOUPROFRESSOR YEMI OSINBAJO LETTER TO YOU
PROFRESSOR YEMI OSINBAJO LETTER TO YOU
 
Presentacion Ardora
Presentacion ArdoraPresentacion Ardora
Presentacion Ardora
 
Ficha Mixto Baja
Ficha Mixto BajaFicha Mixto Baja
Ficha Mixto Baja
 

More from Hafeez Abdulazeez

Unilag Senate Election Result
Unilag Senate Election ResultUnilag Senate Election Result
Unilag Senate Election ResultHafeez Abdulazeez
 
BUHARI ON RELIGION -- ENGLISH
BUHARI ON RELIGION -- ENGLISH BUHARI ON RELIGION -- ENGLISH
BUHARI ON RELIGION -- ENGLISH Hafeez Abdulazeez
 
KNOW YOUR LOCAL GOVERNMENT ELECTORAL OFFICER
KNOW YOUR LOCAL GOVERNMENT ELECTORAL OFFICERKNOW YOUR LOCAL GOVERNMENT ELECTORAL OFFICER
KNOW YOUR LOCAL GOVERNMENT ELECTORAL OFFICERHafeez Abdulazeez
 
A new deal with nigeria apc manifesto
A new deal with nigeria apc manifestoA new deal with nigeria apc manifesto
A new deal with nigeria apc manifestoHafeez Abdulazeez
 
Nigeria Voters transfer guideline 2015
Nigeria Voters transfer guideline 2015Nigeria Voters transfer guideline 2015
Nigeria Voters transfer guideline 2015Hafeez Abdulazeez
 

More from Hafeez Abdulazeez (8)

Unilag Senate Election Result
Unilag Senate Election ResultUnilag Senate Election Result
Unilag Senate Election Result
 
BUHARI ON RELIGION -- ENGLISH
BUHARI ON RELIGION -- ENGLISH BUHARI ON RELIGION -- ENGLISH
BUHARI ON RELIGION -- ENGLISH
 
BUHARI ON RELIGION -- IGBO
BUHARI ON RELIGION -- IGBOBUHARI ON RELIGION -- IGBO
BUHARI ON RELIGION -- IGBO
 
KNOW YOUR LOCAL GOVERNMENT ELECTORAL OFFICER
KNOW YOUR LOCAL GOVERNMENT ELECTORAL OFFICERKNOW YOUR LOCAL GOVERNMENT ELECTORAL OFFICER
KNOW YOUR LOCAL GOVERNMENT ELECTORAL OFFICER
 
Act now training manual
Act now training manualAct now training manual
Act now training manual
 
A new deal with nigeria apc manifesto
A new deal with nigeria apc manifestoA new deal with nigeria apc manifesto
A new deal with nigeria apc manifesto
 
Am i eligible to vote
Am i eligible to vote Am i eligible to vote
Am i eligible to vote
 
Nigeria Voters transfer guideline 2015
Nigeria Voters transfer guideline 2015Nigeria Voters transfer guideline 2015
Nigeria Voters transfer guideline 2015
 

BUHARI ON RELIGION -- YORUBA

  • 1. “A kò gbọdọ lo ẹsìnláti fa ìyapa, láti fi ìyà jẹni, tàbiláti lo àǹfàní tí kò tọ” 4th January, 2015 “Orílẹ-èdè Nàìjíríà tí a ni lọkàn jẹ èyí tí gbogbowa á le jọjòkó ƴọayọ ìdùnnú, kí á dì jọdúpẹ lọwọ Olọrunpapọ. Bí ó ti yẹ kí ó rí nìyẹn” 4th January, 2015 “Ojúṣe ìjọba ni láti pèsè ààbò àti ìfọkàn balẹ fún gbogboọmọ Nàìjíríà láìfi ti ẹsìn, ẹyà àti èdè ṣe. Ohùn tí a gbọdọ pawọpọ ṣe ni, ní pàtàkì jùlọ ní ọjọ òní tí à ń ṣe ìdúpẹ” 4th January, 2015 “Ìgbàgbọ mi láti ìbèrè ayé mí ni wípé gbogbo ọmọ orílẹ-èdè Nàìjíríà gbọgbọ ní òmìnira ẹsìn láti sin Ọlọrun gẹgẹ bí ìgbàgbọ wọn” 4th January, 2015 “Ojúṣe ìjọba kìí ṣe ti ẹsìn” 4th January, 2015. Buhari Nípa Èsìn www.actnow.ng “Inú mi dùn láti ríi wí pé ìsìn ìdúpẹ ọlọdọọdún yìí, bí ó tilẹ jẹ pé ìsìn ẹsìn Kírísítéẹnì ni, síbẹ o kó gbogbo ẹlẹsìn papọ. Kírísítẹnì, Mùsùlùmí àti gbogbo ẹsìn tí ó kù ni wọn ń darapọ níbí lọdọọdún láti dúpẹ lọwọ Ọlọrun. Bí ó ṣe yẹ kí ó rí nìyí” 4th January, 2015. Kín Ni Èrò Bùhárí Nípa Ѐsìn? “Àwòrán fọnrán tí wọn fi sórí ẹrọ agbọrọkáyé fi wọn hàn gẹgẹ bíi elérò kúkúrú. Ó fi irú ènìyàn tí wọn jẹ hàn; irú wọn kò le ṣẹrù bàwá tàbí dúnkokò mọ òmìnira wa . Ọrọ ẹnu wọn ti fi hàn gbangba wí pé wọn kìí ṣe ènìyàn Ọlọrun. Wọn kò ní èrò rere fún ọrílẹ-èdè wa àti àwa ènìyàn ibẹ. Mùsùlùmí ni mi. Mo ní ìmọ ẹsìn kírísítẹnì mo sì mọ wí pé ẹsìn méjéèjì ń wá àgbéjọpọ àlàáfíà fún ọmọ ènìyàn” Vanguard; 8th May, 2014.
  • 2. Ǹjẹ Alákatakítí Ẹsìn Mùsùlùmí Tí Ó Fẹ Sọ Orílẹ-èdè Nàìjíríà Di Ẹlẹsìn Mùsùlùmí ni Buhari? Ní nǹkan bíi ọdún márùn-ún sẹyìn ni wọn bẹrẹ sí ní fi ẹsùn kan Ọgágun Muhammadu Buhari wí pé alákatakítí ẹsìn Mùsùlùmí ni àti wí pé ó fẹ sọorílẹ-èdè yìí di ti ẹlẹsìn Mùsùlùmí. Ẹ jẹ kí á wo àwọn òtítọ tí ó fi ojú hàn: Òtítọ Ibẹ • Bùhárí kò fi ìgbà kan sọ wí pé òun á mú ìṣèjọba nira fún ìjọba ilẹ Nàìjíríà. • Ọkan nínú àwọn Olóyè Ẹgbẹ PDP Alhaji Lawal Kaita ló sọ wí pé ìsàkóṣo ìjọba ilẹ Nàìjíríà á nira látiṣe lẹyìn ìdìbò ọdún 2011. • Irọ ni Rueben Àbàtì tí ó jẹ amúgbálẹgbẹẹ Ààrẹ lórí ètò Ìròyìn pa wí pé Bùhárí ló sọbẹẹ. Kín Ni Bùhárí Ṣe Nípa Irọ Àbàtì Yìí? • Bùhárí pe Àbàtì àti ìwé Ìròyìn Guardian (tí ó tẹìròyìnnáà jáde) ní ẹjọ ìbanilórukọjẹ sí ilé ẹjọ gíga (ṅumber ẹjọ yẹn ni ID837/2011). • Bùhárí gbà láti gbé ẹjọ kúrò nílé ẹjọ nítorí pé Jonathan bẹ Bùhárí. • Ní ọjọ Kọkànlá Oṣù Keje ọdún 2013 (11-7-2013) ìwe] ìròyìn Guardian tẹ àtẹjáde níbití Àbàtì tigbà wí pé irọ niòun pa mọ Bùhárí, ó sì tọrọ àforíjì. Ǹjẹ Bùhárí kórìíra àwọn ẹlẹsìn mìíràn? • Nígbà tí ó jẹ olórí orílẹ-èdè yìí, mọkànlá (11) nínú àwọn Gómìnà mọkàndínlógún (19) tí ó yàn sí ipò Gómìnà, ẹlẹsìn Kírísítẹẹnì niwọn. Púpọ nínú àwọn tọ ń bá Bùhárí siṣẹ àti àwọn òsìṣẹ inú ilé rẹ, kírísítẹẹnì niwọn. • Bùhárí nígbàgbọ wí pé kò yẹkí orílẹ-èdè Nàìjíríà fi aramọ ẹsìn kan ṣoṣo, dípò bẹẹ, kí á fi ààyè gba olúkálukú láti ṣe ẹsìntí ó bá fẹ. Torí ìdí èyí ló ṣe kọ láti jẹ kí Orílẹ-èdè Nàìjíríà darapọ mọ ẹgbẹ Orílẹ-èdè Ẹsìn Mùsùlùmí Agbaiyé (OIC). Bùhárí kò kórìíra àwọn tí kìí ṣe ẹlẹsìn Mùsùlùmí! Olórí tí ó fi ọkàn sin ọrílẹ-èdè Nàìjíríà ni. Ó kó ènìyàn mọra, ó sì tisiṣẹ pọ pẹlú ọpọlọpọ ọmọ Nàìjíríà láìfi ti ẹsìn tàbí ẹyà ṣe. Àwọn olórí méjì tí ó súnmọ Bùhárí dáadáa ni Ọgágun Yàkúbù Gowon àti Theophilus Danjuma GCON. Ẹlẹsìn Kírísítẹnì ni àwọn méjéèji, wọn sì wà láyé, ẹnití ó bá fẹ mọ òtítọ bóyá alákatakítí ẹsìn Mùsùlùmí n iBùhárí tàbí bẹẹ kọ, kí ó lọbí wọn. Kín Ni Bùhárí Sọ Nípa Boko Haram? “Ìwà ìkà nikí á máa fi àdó olóró pa ènìyàn ní gbogbo ìgbà. Ó burú jáì láti huirú ìwà yìí lọjọ ọdún Kérésì, gbogbo ẹni tó bá nífẹẹ àlàáfíà ló yẹkí ó bu ẹnuàtẹ lu iwà ìkà yìí, kí wọnsì bèèrè fún wíwá àwọn ọdaràn wọnyí kànláti fi wọn jófin” Ìwé Ìròyìn This Day Life; 26th December, 2012. “N kò mọ ọmọ ẹgbẹ Boko Haram Kankan. N kò gbàgbọ nínú ìpànìyàn, n kò sì mọ ẹsìn Kankan tí á lọ pa ènìyàn, sun ilé-ẹkọníná” Punch 8th November, 2012 Kínṅi Ó Yẹ Kí O jẹ Ojúṣe Àwọn Olórí Ẹsìn? SỌ ÒTÍTỌ!!! “ahọn gbogbo àwọn wòlíì orílẹ-èdè yìí gbọdọ tú, gbogbo àwọn ẹnu tí a ti padé gbọdọ là, bí wọn bá ti pa ọ lẹnumọ, pọ ohun tí wọn fi dí ọ lẹnu kí o sọrọ nítorí ọjọ iwájú àwọn ọmọ wa - - Bí jíjẹ olórí bàbá mi bá máa mú ìparun bá àwọmọmọ, jẹ kí àjòjì kúkú ṣe olórí kí ìran wasì wà” “Bí baba bá ń jẹ àjẹyó, tí ebi sì ń pa àwọn ọmọ, ǹjẹ irú ẹni bẹẹ yẹní gégé baba bi?” RevF.R. Ejike Mbaka 31st December, 2014 “Àwọn Olùsọ Àgùtànkan ń jẹ àṣáró Jákọbù, wọn sì ń ta àsọtẹlẹ wòlíì: wọn ń fi ìfàmìòróró yàn se òwò ní Aso Rock --- àwọnkanń gbé owó ilẹ wa, wọn ń sọ ọ di owó Dọlà nínú ọkọ òfurufú aládàáni, wọn ń gbé e jáde lọkùrò lórílẹ-èdè” Rev F.R. EjikeMbaka 31st December, 2014